Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

Kíka Bíbélì àti Kíkẹ́kọ̀ọ́ Rẹ̀

Bíbélì Kíkà

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Ka Bíbélì?

Báwo lọ̀pọ̀ èèyàn ti ṣe jàǹfààní látinú kíka Bíbélì?

Ètò Kíka Bíbélì

Ìbáà jẹ́ ètò Bíbélì kíkà ojoojúmọ́ lò ń wá tàbí ti ọdọọdún tàbí èyí tó wà fẹ́ni tó ṣẹ̀ṣẹ̀ fẹ́ máa ka Bíbélì, ètò Bíbélì kíkà yìí máa wúlò fún ẹ.

Báwo Ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?​—Apá Kìíní: Wo Ohun Tó Wà Nínú Bíbélì

Tó bá ṣẹlẹ̀ pé o rí àpótí ìṣura ńlá kan, ó dájú pé ó máa wù ẹ́ láti mọ nǹkan tó wà nínú ẹ̀? Bíbélì ò yàtọ̀ sí àpótí ìṣura. Àwọn ìṣura ọgbọ́n tó pọ̀ gan-an tó sì wúlò ló wà nínú ẹ̀.

Báwo ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?​—Apá Kejì: Jẹ́ Kí Bíbélì Gbádùn Mọ́ Ẹ

Ohun márun-un tó máa jé kó o rí ara ẹ nínú Bíbélì kíkà rẹ.

Báwo Ni Bíbélì Ṣe Lè Ràn Mí Lọ́wọ́?—Apá 3: Túbọ̀ Jàǹfààní Púpọ̀ Bó o Ṣe Ń Ka Bíbélì

Ohun mẹ́rin tó o lè ṣe kó o lè túbọ̀ jàǹfààní púpọ̀ bó o ṣe ń ka Bíbélì.

Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì

Ki Nidi To Fi Ye Ko O Kekoo Bibeli?

Nje o ti ronu ri pe, ‘Mi o ki i raye,’ tabi ‘Mi o feran ki n maa sadehun’?

Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Lóye Bíbélì?

Ọ̀p gbà pé ọba ìwé ni Bíbélì láìmọ bí wọ́n ṣe lè jàǹfààní nínú rẹ̀.

Kí Ló Yẹ Kí O Ṣe Kó O Lè Lóye Bíbélì?

O lè lóye ọ̀rọ̀ pàtàkì tó wà nínú ẹ̀.