Lọ wo ohun tó wà nínú rẹ̀

BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ

Mo Fẹ́ Jà fún Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn

Mo Fẹ́ Jà fún Ẹ̀tọ́ Ọmọnìyàn

 Rafika wọ ẹgbẹ́ ajàfẹ́ẹ̀tọ́-ọmọnìyàn kó lè gbógun ti ìwà ìrẹ́jẹ. Àmọ́, ó wá kọ́ nípa ìlérí tó wà nínú Bíbélì nípa àlááfíà àti ìdájọ́ òdodo lábẹ́ Ìjọba Ọlọ́run.